Friday, March 13, 2020

Yorùbá Se Àmúdópin Èètò Lórí Àmòtékùn

Ajíse Bí Ọ̀yọ́ Làárí, Ọ̀yọ́ Kìí Se Bíí Baba Ẹnìkọ́ọ̀kan. Àìrìnpọ̀ ejò níí j'ọmọ ejò níyà tọ́ká bá dúró, tí sèbé dúró, tí paramọ́lẹ̀ náà tún k'ọ̀rọ̀ ìwọ̀sí, t'éjòlá tíí ṣe baba wọn náà ńwọ́ ruru bọ̀ lẹ́yín wọn, ẹ gbọ́ná, talò tóó gbénà w'ojú ẹkùn láì fòyà?